news_title
stringlengths 17
143
| label
stringclasses 7
values |
---|---|
Arsenal vs Manchester United: Arsenal borí i Manchester United ní Premier league | sport |
9th Assembly: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Femi Gbajabiamila tó di Olórí Ilé Asojú-sòfin Nàìjíríà tuntun | politics |
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀ | entertainment |
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode | nigeria |
Boko Haram video torture: A ṣetán láti fìyà tó tọ́ jẹ ọmọ ogun ti adé ìwà ìbàjẹ́ fídíò náà bá ṣímọ́ lórí | nigeria |
Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye | entertainment |
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ olóṣèlú pàtàkì tó tako Awolọwọ | entertainment |
Emeka Ihedioha: Ibo 273,404 lo ni, ti Nwosu to tẹle si ni ibo 190,364. | politics |
Obìrin kògbérégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá | entertainment |
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn | politics |
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland | nigeria |
Sọ́jà méje wọ gàù lórí ẹ̀sùn olè jíjà ní ìpínlẹ̀ Eko | nigeria |
Biafra at 50: Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà | nigeria |
Adamawa election result: Olùdíje PDP já ipò gómìnà gbà mọ́ gómínà Bindow lọ́wọ́ | politics |
Yollywood: Bákan náà ni àwòrán Sikiratu Sindodo tó ń ṣọjọ́ ìbi, gba orí ayélujára | entertainment |
Offa Bank Robbery: Àwọn afunrasi ní àwọn kò fí t'inu fẹdo jẹwo fún ọlọ́pàá | nigeria |
Nigeria 2019: INEC ìpínlẹ̀ Rivers ṣetán láti kéde èsì ìdìbò Rivers | politics |
NBC ní kí àwọn ilésẹ to tẹ ofin lóju san #500,000 | nigeria |
Arm forces Remeberance day: Naijiria ń ṣe ìrántí àwọn ológun to ṣubú lójú ogun | nigeria |
Imo: Aléjò mẹ́wàá ṣòfò ẹmí níbi ayẹyẹ ìgbéyawó | nigeria |
Orò Festival: 5.30 ìrọ̀lẹ́ si 5.30 ìdájí ní àwọn olórò yóò fi máa yíde ìlú | entertainment |
Ruga Settlement: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani lọ̀nà àbáyọ sí wàhálà àgbẹ̀ àti Fulani | nigeria |
Ibadan Refuse: Kọmísánà fọ́rọ̀ àyíká ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní bó ṣe jẹ́, kò ṣàdédé wáyé | nigeria |
FUTA: Òfin ti wà nílẹ̀ tó ní ká lé akẹ́kọ̀ọ́ tó bá na akẹẹgbẹ́ rẹ̀ | nigeria |
Oyo Grazing Bill: Ilé aṣòfin ní yóò di èèwọ̀ láìpẹ́ láti ta ilẹ̀ fún darandaran | nigeria |
2019 elections update: PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin | politics |
EKIFEST 2019: Ẹkẹ mímù, ayò títa, àfihàn iṣẹ́ ọnà wáyé níbi àjọ̀dún àṣà | entertainment |
Amina Zakari: INEC ní Amina Zakari kọ́ ni yóò wà ní ìdí ìbò kíkà lásìkò ìdìbò 2019 | politics |
Ojúde Ọba: Ayẹyẹ tó ń ṣàfihàn àṣà àjogúnbá Yorùbá | entertainment |
Elephants Death: Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn | entertainment |
Ààrẹ Gani Adams: Olùdíje tó bá ṣetán lórí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ni Yorùbá yóò dìbò fún | politics |
Child marriage: $3,500 la gbà láti fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ | world |
2019 Election: INEC sòfin láti dènà fífi owó ràbò níbi ìdìbò 2019 | politics |
Buhari Resign: Secondus ní kí Buhari kéde nǹkan ò fararọ lẹ́ka ààbò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ kó kọ̀wé fipò sílẹ̀ | politics |
JOHESU: L'Oṣogbo, àwọn òṣìṣẹ́ iléèwòsàn LAUTECHTH wọ́de lórí àìsan owó oṣù | health |
2019 Elections: Ìyàwó Atiku ní dídùn lọsàn yóò so fún ọkọ òun | politics |
Pinnick: Àwọn ọ̀tá mi ló fẹ́ b'orúkọ mi jẹ́ | sport |
Hot mic moment: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé | world |
2023 presidency: Ààrẹ Buhari ní òun kò leè dá sí ètò yíyan ààrẹ tuntun lọ́dún 2023 | politics |
APC Crisis: Àwọn jàndùkú kọlu Ọba Eko àti Gomina ìpínlẹ̀ Edo lọ́nà ilé Oshiomole | politics |
Governorship election update: PDP ní ẹgbẹ́ òun ló ń mókè láwọ̀n ìpínlẹ̀ tí ìbò kó ti parí | politics |
Kano couple: Bí ìyàwó mi ẹni ọdún 84 bá bí ìbejì, Hussaina ati Hassana la ó sọ wọ́n | nigeria |
Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú | entertainment |
BBC Africa Eye: Ìyá mi, bí mo bá rántí ikú rẹ lásìkò ìrọbí, àìbímọ tèmí ń pa mí kú díẹ̀díẹ̀ | entertainment |
Sri Lanka attack: Orílẹ̀èdè mẹjọ, yàtọ̀ sí Sri lanka ló pàdánù èèyàn wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà | world |
Aisha Buhari: Àwọn alágbára ti já ìjọba gbà mọ́ ọkọ mi lọ́wọ́ | politics |
Nigeria 2019 Elections: Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ? | politics |
June 12: Ọjọ́ tí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà, èdè àti ẹlẹ́sìnjẹ̀sìn tó wà ní Nàíjíríà papọ̀ di ọ̀kan | politics |
Broadcasting Service of Ekiti State di ṣíṣí padà lẹ́yìn oṣù máàrùn | entertainment |
Saudi Arabia oil attack: Buhari ní ojú Nàìjíríà ti rí ohun tí Saudi Arabia ń rí báyìí | world |
COZA RAPE: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò | entertainment |
Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà | health |
Wizkid: 'Ọfẹ ní hug'; Ṣé Wizkid yóò fẹ padà wá kọrin ní Ilorin mọ pẹlú òun tí ojú rẹ rí | entertainment |
Egypt President: Aàrẹ Morsi torílè-èdè Egypt dákú,ó gba ibẹ̀ derò alákeji | africa |
Kogi & Bayelsa Polls: Buhari ní ìdìbò gómìnà gbọdọ̀ lọ nírọwọ́ rọsẹ̀ | politics |
Sotitobire: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Kẹta ọdún 2020 | nigeria |
LUTH: Nítorí àìsan owó oṣù, àwọn dókítà ARD da iṣẹ́ sílẹ̀ ní ilé ìwòsàn LUTH nílùú Èkó | health |
Ondo state: Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò nílùú Akure | nigeria |
Kí ló mú kí àwọn ọ̀yìnbó aláwọ̀ funfun gé'run Dàda ọmọ aláwọ̀dúdú? | world |
Algon Oyo: Àwọn ọlọ́pàá ẹnu ọ̀nà káńṣù náà ṣetán láti wọ́n eṣinṣin tó bá ta fírí | nigeria |
Toyosi Adesanya: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kwara ní àwọn àti Fijilanté wà nínú igbó láti ṣàwárí ọ̀daràn tó ṣèkọlù náà | nigeria |
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun | entertainment |
Osun Kidnapping: Àwọn afunrasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé nńú bọ́ọ̀sì Osogbo sí Abuja | nigeria |
Ààrẹ Beji Caid Essebsi, torílẹ̀èdè Tunisia jáde fáyé | africa |
Bullion Van: Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Akure faraya lẹ́yìn tí ọkọ̀ akówó sálọ lẹ́yìn tó pa okùnrin kan | nigeria |
Ilé aṣòfin àgbà: Ìsìnmi olóṣù méjì wa kò le è ṣàkóbá fún àyẹ̀wò mínísítà | nigeria |
Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ | nigeria |
Lagos-Ibadan Express Road: Ìjọba àpapọ̀ ní òun yóò ṣí ọ̀nà tó tì padà ní Dec 15 fọ́dún Kérésì | nigeria |
God support stealing' fídíò ọlọ́pàá tó n da orí ayélujára rú'? | nigeria |
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá | nigeria |
Budget 2020: Ilé aṣòfin àgbà buwọ́lu àbá ìṣúná N10.59trn fún ọdún 2020 | nigeria |
#6thAFRIMA: Burnaboy, 2baba, tiwa Savage àti Wizkid da ilẹ̀ rú ní AFRIMA | entertainment |
Governorship Election Updates: Ajimọbi gba Makinde nimọran lati gbaradì fún iṣẹ́ ńla | politics |
Moroccan Journalist: Hajar Raissouni de èrò ẹwọn lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́ | africa |
Dapchi: Àwọn akẹgbẹ́ Leah Sharibu padà sí ilé ìwé, ṣùgbọ́n Leah kò bá wọn wọlé | nigeria |
Soyinka: Háà, ó ṣe. Ìran mi já Nàìjíríà kulẹ̀ | nigeria |
2019 El;ections: Ìjàmbá iná tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ń kọ àjọ INEC lóminú | politics |
Adeleke vs Oyetola: Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dájọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018 | politics |
Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ | world |
PDP sí Buhari: Gbájú mọ́ ìṣèjọba rẹ ní, yé dùnkokò mọ́ alátakò àti oníròyìn | politics |
BBNaija 2019: Gedoni kúrò ní BBNaija. Khafi bu sẹ́kún | entertainment |
Naira Marley: Pásítọ̀ Omatsola tún kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ láti yé pe ara wọn ní Marlians | entertainment |
Simon Lalong: Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ni ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba òun gbọ̀dọ̀ yan ẹranko kan láàyò | politics |
Police Attack: Ọ̀bẹ ni ọkùnrin kan fi pa Ọlọpàá mẹrin ni Paris | world |
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà | politics |
Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mò ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi | nigeria |
Isabel dos Santos: Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ | africa |
Sudan: Àwọn olórí Sudan bẹ Amẹrika pé kó yọ ọ́ kúrò nínú àwọn orílẹ́-èdè agbésùnmọ̀mí | world |
Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun - NMA | health |
2019 elections: INEC ní òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó sá lọ kò ní gbowó iṣẹ́ rẹ̀ | politics |
Ọgọ́rùn ún èèyàn tí pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìkọlù Zamfara | nigeria |
Kogi, Bayelsa Governorship Elections: INEC kéde ọjọ́ tuntun | politics |
#SagamuOnFire: Àwọn ẹbí Tiamiyu bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn | nigeria |
Obasanjo: Ìdùnnú ọmọ Nàìjíríà ló jẹ́ mí lógún ní 2019 | politics |
Election 2019: Afẹ́nifẹ́re pín nítorí Buhari àti Atiku | politics |
Nigeria 2019 Elections: Kíni o mọ̀ nípa Jimi Agbaje tó ń díje fún gómìnà ìpínlẹ̀ Eko | politics |
Nollywood: Bàbá Sàlá, Ọmọgé Campus, Ajimajasan àtàwọn òṣèré mí ì jáde láyé ní 2018 | entertainment |
Àwọn ará àdúgbó Lekki rí orí àti ara ọkùnrin mẹ́ta ní àdúgbo wọn | nigeria |
FGM: Èyí ni bí àwọn obìnrin kan ṣe n fi abẹ̀ dídá sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì | health |
Ooni: EFCC, ẹ se àtúnse sí ìgbé ayé àwọn ọdaràn tẹ bá mú | nigeria |