news_title
stringlengths
17
143
label
stringclasses
7 values
Arsenal vs Manchester United: Arsenal borí i Manchester United ní Premier league
sport
9th Assembly: Àwọn ohùn tó yẹ kí ẹ mọ nípa Femi Gbajabiamila tó di Olórí Ilé Asojú-sòfin Nàìjíríà tuntun
politics
Ìtàn Mánigbàgbé: Ìnà ẹgba mẹ́sàn-án ni Jesu Oyingbo fi ń kí ọmọ ìjọ ọ́kùnrin tuntun káàbọ̀
entertainment
Ilé ẹjọ́ pàṣẹ kí EFCC gbẹ̀sẹ̀ lé àpò àsùwọ̀n kan tó ní nkan ṣe pẹ̀lú Akinwumi Ambode
nigeria
Boko Haram video torture: A ṣetán láti fìyà tó tọ́ jẹ ọmọ ogun ti adé ìwà ìbàjẹ́ fídíò náà bá ṣímọ́ lórí
nigeria
Nollywood: Joke Silva ní ọkọ òun ni ìtànsán òòrùn tó ṣe iyebíye
entertainment
Ìtàn Mánigbàgbé: Samuel Ladoke Akintọla jẹ́ olóṣèlú pàtàkì tó tako Awolọwọ
entertainment
Emeka Ihedioha: Ibo 273,404 lo ni, ti Nwosu to tẹle si ni ibo 190,364.
politics
Obìrin kògbérégbè mẹ́ta nínú òṣèré Yorùbá
entertainment
Wo àwọn ìlérí tàwọn Gómìnà tuntun ṣe nínú ìbúra wọn
politics
Ọkọ̀ akérò BRT gbiná lórí afárá 3rd Mainland
nigeria
Sọ́jà méje wọ gàù lórí ẹ̀sùn olè jíjà ní ìpínlẹ̀ Eko
nigeria
Biafra at 50: Èyí ni bí ogun abẹ́lé Biafra ṣe bẹ̀rẹ̀ ní Nàìjíríà
nigeria
Adamawa election result: Olùdíje PDP já ipò gómìnà gbà mọ́ gómínà Bindow lọ́wọ́
politics
Yollywood: Bákan náà ni àwòrán Sikiratu Sindodo tó ń ṣọjọ́ ìbi, gba orí ayélujára
entertainment
Offa Bank Robbery: Àwọn afunrasi ní àwọn kò fí t'inu fẹdo jẹwo fún ọlọ́pàá
nigeria
Nigeria 2019: INEC ìpínlẹ̀ Rivers ṣetán láti kéde èsì ìdìbò Rivers
politics
NBC ní kí àwọn ilésẹ to tẹ ofin lóju san #500,000
nigeria
Arm forces Remeberance day: Naijiria ń ṣe ìrántí àwọn ológun to ṣubú lójú ogun
nigeria
Imo: Aléjò mẹ́wàá ṣòfò ẹmí níbi ayẹyẹ ìgbéyawó
nigeria
Orò Festival: 5.30 ìrọ̀lẹ́ si 5.30 ìdájí ní àwọn olórò yóò fi máa yíde ìlú
entertainment
Ruga Settlement: Iléeṣẹ́ ààrẹ ní àgbékalẹ̀ àgọ́ Fulani lọ̀nà àbáyọ sí wàhálà àgbẹ̀ àti Fulani
nigeria
Ibadan Refuse: Kọmísánà fọ́rọ̀ àyíká ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà ní bó ṣe jẹ́, kò ṣàdédé wáyé
nigeria
FUTA: Òfin ti wà nílẹ̀ tó ní ká lé akẹ́kọ̀ọ́ tó bá na akẹẹgbẹ́ rẹ̀
nigeria
Oyo Grazing Bill: Ilé aṣòfin ní yóò di èèwọ̀ láìpẹ́ láti ta ilẹ̀ fún darandaran
nigeria
2019 elections update: PDP pè fún ìwọ́gilé èsì ìdìbò ààrẹ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rin
politics
EKIFEST 2019: Ẹkẹ mímù, ayò títa, àfihàn iṣẹ́ ọnà wáyé níbi àjọ̀dún àṣà
entertainment
Amina Zakari: INEC ní Amina Zakari kọ́ ni yóò wà ní ìdí ìbò kíkà lásìkò ìdìbò 2019
politics
Ojúde Ọba: Ayẹyẹ tó ń ṣàfihàn àṣà àjogúnbá Yorùbá
entertainment
Elephants Death: Erin mẹ́fa d'olóògbé níbi tí wọ́n ti fẹ́ dóòlà ẹ̀mí ara wọn
entertainment
Ààrẹ Gani Adams: Olùdíje tó bá ṣetán lórí àtúntò ìlànà ìṣèjọba ni Yorùbá yóò dìbò fún
politics
Child marriage: $3,500 la gbà láti fa ọmọ ọdún márùn-ún f'ọ́kọ
world
2019 Election: INEC sòfin láti dènà fífi owó ràbò níbi ìdìbò 2019
politics
Buhari Resign: Secondus ní kí Buhari kéde nǹkan ò fararọ lẹ́ka ààbò, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ kó kọ̀wé fipò sílẹ̀
politics
JOHESU: L'Oṣogbo, àwọn òṣìṣẹ́ iléèwòsàn LAUTECHTH wọ́de lórí àìsan owó oṣù
health
2019 Elections: Ìyàwó Atiku ní dídùn lọsàn yóò so fún ọkọ òun
politics
Pinnick: Àwọn ọ̀tá mi ló fẹ́ b'orúkọ mi jẹ́
sport
Hot mic moment: Àwọn ìlúmọ̀ọ́ká olórí orílẹ́-èdè tó sọ̀rọ̀ fẹnu kọ pẹ̀lú ẹ̀rọ gbohùngbohùn rèé
world
2023 presidency: Ààrẹ Buhari ní òun kò leè dá sí ètò yíyan ààrẹ tuntun lọ́dún 2023
politics
APC Crisis: Àwọn jàndùkú kọlu Ọba Eko àti Gomina ìpínlẹ̀ Edo lọ́nà ilé Oshiomole
politics
Governorship election update: PDP ní ẹgbẹ́ òun ló ń mókè láwọ̀n ìpínlẹ̀ tí ìbò kó ti parí
politics
Kano couple: Bí ìyàwó mi ẹni ọdún 84 bá bí ìbejì, Hussaina ati Hassana la ó sọ wọ́n
nigeria
Busola Dakolo: Mílíọ́nù mẹ́wàá náírà tí a béèrè kì í ṣe owó gbà má-bínú
entertainment
BBC Africa Eye: Ìyá mi, bí mo bá rántí ikú rẹ lásìkò ìrọbí, àìbímọ tèmí ń pa mí kú díẹ̀díẹ̀
entertainment
Sri Lanka attack: Orílẹ̀èdè mẹjọ, yàtọ̀ sí Sri lanka ló pàdánù èèyàn wọn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ náà
world
Aisha Buhari: Àwọn alágbára ti já ìjọba gbà mọ́ ọkọ mi lọ́wọ́
politics
Nigeria 2019 Elections: Èwo nínú ìlérí tí Buhari ṣe ní 2015 ló ti mú ṣẹ?
politics
June 12: Ọjọ́ tí ọ̀pọ̀ ẹ̀yà, èdè àti ẹlẹ́sìnjẹ̀sìn tó wà ní Nàíjíríà papọ̀ di ọ̀kan
politics
Broadcasting Service of Ekiti State di ṣíṣí padà lẹ́yìn oṣù máàrùn
entertainment
Saudi Arabia oil attack: Buhari ní ojú Nàìjíríà ti rí ohun tí Saudi Arabia ń rí báyìí
world
COZA RAPE: Ilé ọlọpàá ìlú Abuja pé Fatoyinbo fún ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
entertainment
Fọ́tò ló ṣàfihàn ibi tí ọmọ ti Nọọsi jígbé lódún 1997 wà
health
Wizkid: 'Ọfẹ ní hug'; Ṣé Wizkid yóò fẹ padà wá kọrin ní Ilorin mọ pẹlú òun tí ojú rẹ rí
entertainment
Egypt President: Aàrẹ Morsi torílè-èdè Egypt dákú,ó gba ibẹ̀ derò alákeji
africa
Kogi & Bayelsa Polls: Buhari ní ìdìbò gómìnà gbọdọ̀ lọ nírọwọ́ rọsẹ̀
politics
Sotitobire: Iléẹjọ́ ṣún ìgbẹ́jọ́ síwájú di ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù Kẹta ọdún 2020
nigeria
LUTH: Nítorí àìsan owó oṣù, àwọn dókítà ARD da iṣẹ́ sílẹ̀ ní ilé ìwòsàn LUTH nílùú Èkó
health
Ondo state: Bàbá ọlọ́mọ méjì kú sínú àgbàrà òjò nílùú Akure
nigeria
Kí ló mú kí àwọn ọ̀yìnbó aláwọ̀ funfun gé'run Dàda ọmọ aláwọ̀dúdú?
world
Algon Oyo: Àwọn ọlọ́pàá ẹnu ọ̀nà káńṣù náà ṣetán láti wọ́n eṣinṣin tó bá ta fírí
nigeria
Toyosi Adesanya: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní Kwara ní àwọn àti Fijilanté wà nínú igbó láti ṣàwárí ọ̀daràn tó ṣèkọlù náà
nigeria
Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
entertainment
Osun Kidnapping: Àwọn afunrasí darandaran jí èèyàn mẹ́rìnlá gbé nńú bọ́ọ̀sì Osogbo sí Abuja
nigeria
Ààrẹ Beji Caid Essebsi, torílẹ̀èdè Tunisia jáde fáyé
africa
Bullion Van: Àwọn ọ̀dọ́ ìlú Akure faraya lẹ́yìn tí ọkọ̀ akówó sálọ lẹ́yìn tó pa okùnrin kan
nigeria
Ilé aṣòfin àgbà: Ìsìnmi olóṣù méjì wa kò le è ṣàkóbá fún àyẹ̀wò mínísítà
nigeria
Community Policing: ìjọba ìbílẹ kọọkan yóò gbà ààdọta òsìsẹ
nigeria
Lagos-Ibadan Express Road: Ìjọba àpapọ̀ ní òun yóò ṣí ọ̀nà tó tì padà ní Dec 15 fọ́dún Kérésì
nigeria
God support stealing' fídíò ọlọ́pàá tó n da orí ayélujára rú'?
nigeria
RUGA: Adeboye ní àsìkò tó láti wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ ètò pápá ìjẹko RUGA pátápátá
nigeria
Budget 2020: Ilé aṣòfin àgbà buwọ́lu àbá ìṣúná N10.59trn fún ọdún 2020
nigeria
#6thAFRIMA: Burnaboy, 2baba, tiwa Savage àti Wizkid da ilẹ̀ rú ní AFRIMA
entertainment
Governorship Election Updates: Ajimọbi gba Makinde nimọran lati gbaradì fún iṣẹ́ ńla
politics
Moroccan Journalist: Hajar Raissouni de èrò ẹwọn lórí ẹ̀sùn àgbèrè àti oyún ṣíṣẹ́
africa
Dapchi: Àwọn akẹgbẹ́ Leah Sharibu padà sí ilé ìwé, ṣùgbọ́n Leah kò bá wọn wọlé
nigeria
Soyinka: Háà, ó ṣe. Ìran mi já Nàìjíríà kulẹ̀
nigeria
2019 El;ections: Ìjàmbá iná tó ń wáyé lemọ́lemọ́ ń kọ àjọ INEC lóminú
politics
Adeleke vs Oyetola: Ilé ẹjọ́ kòtẹmilọ́rùn yóò dájọ́ ìdìbò gómìnà Oṣun ọdún 2018
politics
Wo àwọn orílẹ̀èdè tí wákàtí ààwẹ̀ wọn gùn ju ti Nàìjíríà lọ
world
PDP sí Buhari: Gbájú mọ́ ìṣèjọba rẹ ní, yé dùnkokò mọ́ alátakò àti oníròyìn
politics
BBNaija 2019: Gedoni kúrò ní BBNaija. Khafi bu sẹ́kún
entertainment
Naira Marley: Pásítọ̀ Omatsola tún kìlọ̀ fáwọn ọ̀dọ́ láti yé pe ara wọn ní Marlians
entertainment
Simon Lalong: Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau ni ẹni tó bá fẹ́ ipò ní ìjọba òun gbọ̀dọ̀ yan ẹranko kan láàyò
politics
Police Attack: Ọ̀bẹ ni ọkùnrin kan fi pa Ọlọpàá mẹrin ni Paris
world
Fayemi: Gbèsè tí mo bá nílẹ̀ ni kò jẹ́ kí n ti yan kọmíṣọ́nà
politics
Trafficking in Abuja: Ọkùnrin 15 ni mò ń ba sùn lọ́ọ̀jọ áti san owó ọ̀gá mi
nigeria
Isabel dos Santos: Obìnrin tó lówó jùlọ ní Africa 'ja orílẹ̀-èdè rẹ̀, Angola lólè' fi kó ọ̀rọ̀ jọ
africa
Sudan: Àwọn olórí Sudan bẹ Amẹrika pé kó yọ ọ́ kúrò nínú àwọn orílẹ́-èdè agbésùnmọ̀mí
world
Owó làwọn olóṣèlú mọ̀ ni wọ́n ṣe fẹ́ kí dókítà lọ sókè òkun - NMA
health
2019 elections: INEC ní òṣìṣẹ́ rẹ̀ tó sá lọ kò ní gbowó iṣẹ́ rẹ̀
politics
Ọgọ́rùn ún èèyàn tí pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìkọlù Zamfara
nigeria
Kogi, Bayelsa Governorship Elections: INEC kéde ọjọ́ tuntun
politics
#SagamuOnFire: Àwọn ẹbí Tiamiyu bèrè fún ìwádìí tòótó lórí ikú ọmọ wọn
nigeria
Obasanjo: Ìdùnnú ọmọ Nàìjíríà ló jẹ́ mí lógún ní 2019
politics
Election 2019: Afẹ́nifẹ́re pín nítorí Buhari àti Atiku
politics
Nigeria 2019 Elections: Kíni o mọ̀ nípa Jimi Agbaje tó ń díje fún gómìnà ìpínlẹ̀ Eko
politics
Nollywood: Bàbá Sàlá, Ọmọgé Campus, Ajimajasan àtàwọn òṣèré mí ì jáde láyé ní 2018
entertainment
Àwọn ará àdúgbó Lekki rí orí àti ara ọkùnrin mẹ́ta ní àdúgbo wọn
nigeria
FGM: Èyí ni bí àwọn obìnrin kan ṣe n fi abẹ̀ dídá sọ ara wọn di 'fágìn' lẹ́ẹ̀kejì
health
Ooni: EFCC, ẹ se àtúnse sí ìgbé ayé àwọn ọdaràn tẹ bá mú
nigeria