news_title
stringlengths
17
143
label
stringclasses
7 values
Coronavirus: Nàìjíríà sọ àgádágodo sí ilé ìtajà China l‘Abuja láti dènà ìtànkálẹ̀ Coronavirus
health
Oluwo: Oluwo fárígá pẹ̀lú ìjọba àpapọ̀ lórí àgbékalẹ̀ iléèwé ẹ̀kọ́ṣẹ́ olùkọ́ni
nigeria
AFCON 2019: Àmì ayò tí Nàíjíríà àti South Afrika gbá rèé
sport
Ajimobi: Orúkọ èmi, Akala, Ladoja, Adebayo Faleti àtàwọn míì
politics
Deji Adeyanju: Àwọn olólùfẹ́ Ààrẹ Buhari kọlu Deji Adeyanju àtàwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́ tó wọ́de l'Abuja
politics
Tí mo bá rí obìnrin tó kò níṣẹ́ lápá, mó máa ń ní kí wọ́n wò mí ṣe àríkọ́gbọ́n
nigeria
YCE: Ìpínlẹ kọ̀ọ̀kan ní àṣẹ láti dá ààbò bo àwọ̀n ènìyàn wọn
nigeria
Davido: Àpètàn orukọ̀ ọmọ tuntun náà ní David Adedeji Ifeanyi Adeleke
entertainment
Daddy Freeze: 'Kátàkárà ni owó orí gbígbà lórí ọmọbìnrin jẹ́'
entertainment
Libya Refugees: Àtìpó 162 míì dé padà láti Libya
africa
Mínísítà 43 ni Ààrẹ Muhammadu Buhari ṣe ìbúra fún to yàn sípò
politics
ASSU Strike: Ìpàdé ASUU àti ìjọba tún forí sánpọ́n
nigeria
Yollywood: Odunlade fijó bẹ́ẹ, Lizzy padà sọ́dún 2012, Lateef gbàmì ẹ̀yẹ tuntun
entertainment
Sanwo-Olu: Àtàrí Àjànàkú ni àkóso Eko, kì í ṣe ẹrù ọmọdé
politics
Seyi Makinde: Gbogbo iṣẹ́ àgbàṣe tí Ajimọbi ṣe lẹ́yìn ìbò ní màá gbéyẹ̀wò
politics
Ondo police: Ìwádìí ń tẹ̀síwájú lórí ìjínigbé náà
nigeria
Nigeria Elections 2019: Dapo Abiodun, ǹkan márùn ún tó yẹ kẹ́ẹ mọ̀ nípa rẹ̀
politics
Afenifere: Ìgbà wo ni Bola Tinubu di ọmọ ẹgbẹ Afenifere?
politics
Oluwo: Ó dàbí ẹni pé ọ̀tá pọ̀ fún mi, inú wọn kò dùn sí bí mo ṣe ń ṣakọ
entertainment
Gani Adams: Kò bá dáa tí INEC bá sùn ọjọ́ gbígba PVC síwájú
politics
Mọ̀ síi nípa Yakubu tó wọ bàtà tí Jẹ́gà bọ́ sílẹ̀ ni INEC
politics
Adewale Ayuba: Ogun ń ja àgbo Fújì, ni wọ́n ṣe ń jà
entertainment
BOWEN: Àwọn adarí ti fásitì Bowen pa lẹ́yìn wàhálà àwọn akẹ́kọ̀ọ́
nigeria
Lagos crime: Àáfà ní òun bu ọlọ́pàá jẹ nígbà tó fẹ́ yí òun lọ́rùn ní Mushin
nigeria
NLC: Gbogbo òṣiṣẹ ló n fẹ́ ilọsiwaju Naijiria
nigeria
ICPC vs Kashamu: Irọ́ ni ICPC ń pa mọ́ Kashamu lórí ọ̀rọ̀ ọkọ̀ áńbúlàǹsì àti ẹ̀rọ amúnáwá
nigeria
Tinubu 2023': 'Èmi kọ́ lò rán ẹgbẹ́ 'Asiwaju Reloaded Ambassadors' níṣẹ́ o'
politics
Lassa fever: Ìjọba Eko ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ebonyi tó wá kẹ́kọ́ ìmọ̀ òfin, ní wọ́n bá Lassa lára rẹ̀
health
Lagos Building Collapse: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko gbé ìgbìmọ̀ olùwádìí kalẹ̀
nigeria
Man Utd Vs Man City: Kò ṣèlẹ́rí! àwọn alatilẹyin Liverpool yóò gbè lẹyìn Man Utd
sport
Akure Anglican Bursar: Àwọn agbébọn gbé owó sálọ lẹ́yìn tí wọ́n pa akápò ìjọ Anglican
nigeria
NNPC: Ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀ lórí ohun tó fa ìjàmbá iná ọ̀pá epo tó wáyé l'Abule Egba
nigeria
Herbal Medicine: Gbígboyè fásítì nínú iṣẹ́ ìṣègùn ìbílẹ̀ dára, àrídájú gbọdọ̀ wà lórí rẹ̀
health
Ìdílé kan gbé ilé iṣẹ́ ọkọ̀ òfurufú lọ ilé ẹjọ́ lẹ́yìn tí wọ́n léwọ̀n dànù nínú ọkọ̀ pé ara wọ́n ń rùn
world
Kogi Election: Dino Melaye náà pariwo pé àwọn apanìyàn ti gbòde ní ìbò ku ọ̀la
politics
Osun Politics: Aregbesola ní irọ́ n'ìròyìn tó ń sọ pé aáwọ̀ wà láàrín òun àti gómìnà Oyetola
politics
Atiku: Màá foríji àwọn tó bá dá owó ìlú tí wọ́n kó jẹ padà
politics
Yewande Oyediran: Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀
nigeria
Ẹ̀ wo àwòrán ìgbé ayé Robert Mugabe!
africa
Illegal Orphanage: Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira
nigeria
NLC Strike: Mínísítà fọ́rọ̀ òṣíṣẹ́ pe ìpàdé àwọn olórí òṣìṣẹ́ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
nigeria
Ìgbìmọ̀ iṣedajọ orílè-èdè Nàìjíríà NJC nikan lo le yọ adajọ-Amofin
nigeria
DR Congo: Àwùjọ àgbáyé ń polongo àláàfíà nítorí èsì ìdìbò ààrẹ
africa
Chioma Ikeaza-Uzodinma tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ búra wọlé fún ọkọ rẹ̀ ní Imo
politics
Sex for Grades: Fásitì Eko ní kí olùkọ́ míì lọ fìdímọ́lé lori Fídíò BBC
nigeria
Lagos State: Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ní irọ́ ni àjọ EIU ń pa pé ìlú Eko ló léwu jùlọ láti gbé lágbàáyé
nigeria
Ààrẹ Donald Trump: Qasem Soleimani ń gbìmọ̀ràn láti kọ lù wá l'Amerika la ṣe kọ́kọ́ yára pa á - Trump Ààrẹ
world
Kogi àti Bayelsa: Gomina Yahaya Bello ti Kogi àti David Lyon ti Bayelsa gba ìwé ẹ̀rí INEC
politics
Toyin Abraham: Àwọn ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa Toyin Abraham
entertainment
Omolola Ajayi: Gloria Bright ní ọ̀gá òun kọ̀ láti sanwó oṣù fún òun lẹ́yìn oṣù mẹ́ta
entertainment
Female Driver: Sokunbi ni obìnrin àwakọ̀ Dáńfó l‘Eko, tó ń lọ̀ láti ìpínlẹ̀ kan sí òmíì
nigeria
Amotekun: Ìjọba Eko kéde pé òun ní ẹ̀ṣọ́ aláàbò tẹ́lẹ̀, òun kò sí ní yí orúkọ rẹ̀ padá sí Amotekun
nigeria
Irú kí leyi,iná jó òkú méjìlá mọ inú ílé ìgbókúpamọ́sí OAU
nigeria
Ibadan High Chiefs: Àwọn Olóyè Ibadan mọ́kànlélógún tó ń pe ara wọn lọ́ba ń fi ẹ̀wọ̀n run imú
entertainment
Prophecy 2020: Primate Ayodele, Baba Adeboye àti Father Mbaka sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa 2020!
nigeria
University of Transportation Daura: Nǹkan mẹ́wàá tó yẹ ní mímọ̀ nípa fásitì ẹ̀kọ́ ìrìnnà
nigeria
Amẹrika dá akẹ́kọ́ọ̀ Harvard pada sí orílẹ̀-èdè rẹ̀ nítori ǹkan ọ̀rẹ́ rẹ̀ kọ lóri ayálujára
world
Ooni: Mo rọ àwọn àgbẹ̀ àti darandaran láti gba ìrẹ́pọ̀ láàyè
nigeria
Kaduna Kidnapping - Ọmọ iléèwé mẹfà pẹlú Olùkọ méjì ni wọn jígbé ni Kaduna.
nigeria
Akitoshi Okamoto: Òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì, wọ gbaga ọlọ́pàá torí pé o pé ní 24,000
nigeria
Yollywood: Àwọn èèyàn fèsì pé Kemi ń díbọ́n ni, tórí ọ̀rọ̀ ọkùnrin ni
entertainment
PDP: A ò fẹ́ ẹ̀jẹ̀ Buhari gẹ́gẹ́ bí alábojútó ìbò kíkà
politics
#Zamfarakillings: Ìjọba pàṣẹ kí wọn dáwọ́ ìwakùsà ní Zamfara
nigeria
R Kelly: Èmi kò jẹ̀bi ẹ̀ṣùn fífi ipá bá ọmọdé lòpọ̀
entertainment
America: Ẹ má dúró ju ìṣẹ́jú mẹ́wàá lọ níta ìlú yóò tutù kọjá àlà
world
Lizzy Anjorin: Ẹ má bú mi, ọ̀pọ̀ òṣèré tíátà ni kìí bá mi yọ̀ fún ire mi
entertainment
Ìtàn Mánigbàgbé: £100, tíí ṣe ₦42,150 àsìkò yìí, nìjọba fun Taiwo Akinkunmi lówó iṣẹ́ lọ́dún 1959
entertainment
Kí gan an ni ẹgbẹ́ NURTW ní ṣe pẹ̀lú òṣèlú Nàìjíríà?
politics
El-Zakzaky pé ìpàdé pẹ̀lú àwọn àgbẹ́joro India àti àwọn àjọ ti kìí ṣe ti ìjọba
nigeria
Marriage Certificate: Bí o ṣe lè mọ ìgbéyàwó tí kò bá òfin mu
entertainment
Aláàfin ìlú Oyo ti bímọ okùnrin tuntun lẹ́ni odún 81
entertainment
N11trn subsidy: Ǹjẹ́ ẹ mọ̀ pé owó ìrànwọ́ epo lè kọ Second Niger Bridge méjìléláàdọ́ta?
nigeria
Burger: Kunle Afod, Sindodo, Lola Alao se ìdárò ẹni to lọ
entertainment
Àjọ Fifa fòfin de Samson Siasia títí láíláí
sport
Lórí ọ̀rọ̀ Pásítọ̀ COZA àti Dakolo, Ìwadìí ń tẹ̀ síwájú, ṣùgbọ́n a kò mọ ohunkohun nípa rẹ̀ mọ́- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Èkó
entertainment
Sasa Market: Seriki Hausa ní ogún èèyàn ló farapa nínú ìjà Ṣasa
nigeria
Àwọn agbófinró ń wá ọlọ́pàá tó yìnbọn lu olólùfẹ̀ẹ́ méjì, lẹ́yìn tí wọ́n gbé akẹgbẹ́ẹ̀ rẹ̀
nigeria
Lagos Fire Service: Ẹ máse tan àbẹ́là lórí ike tàbí pákó
nigeria
Birth tourism: Ẹ̀yin obìnrin tẹ́ẹ fẹ́ wá bímọ ní America, ọ̀nà ti tì pa látònì! - Trump
world
INEC: Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú yóò dìbò àbẹ́lé lóṣù Kẹjọ
politics
Kunle Afod: Ohun mẹ́wàá tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa Kunle Afod ti Yollywood
entertainment
Olùkọ kan àti àwọn mẹ́ẹ̀dógún míràn ni wọn ti yẹgi fún ní Bangladesh
world
9th Assembly: Èrò ṣe ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí ẹní tí àṣẹ ilé aṣòfin àgbà Nàìjíríà yóò já mọ́ lọ́wọ́
politics
Adio Atawẹwẹ: Orin Fuji ló gba iwé kíkà lọ́wọ́ mi
entertainment
Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n - Ó ń rọ̀ wá láti má se kọjá agbára wa
entertainment
Carabao cup: Iheanacho gba góòlù wọlé láti ra Leicester city padà lọ́wọ́ ìfìdírẹmi
sport
Supreme court judgement: Ta ni Gómìnà Bala Mohammed?
nigeria
Ilé Aṣòfin Eko: A fẹ́ mọ̀ bí Ambode ṣé nà ₦45b tó fi ra BRT
nigeria
Kogi àti Bayelsa: Èsì ìbò tó jáde láti ìpínlẹ̀ Kogi
politics
ECOWAS: Buhari nàka àbùkù s'orílẹ̀èdè Libya látàrí aàbò tó mẹ́hẹ l'Afrika
africa
#BBCNigeria2019: Ààrẹ Buhari ní ìdìbò ọjọ́ Àbámẹ́ta yóò lọ n'ìrọwọ́ rọsẹ̀
politics
Gas Explosion: Ènìyàn márùn ún ti jáláìsí látàri ìjàmbá afẹfẹ gáàsì Kaduna
nigeria
Léyìn òpọ̀lọ̀pò ọdún àgbàọ̀jẹ̀ agbábọ́ọ̀lù ọmọ Cameroun ní òun ti dé wáàsimi
africa
Amole festival in Akure: Deji pàṣẹ kí gbogbo ọjà àti ṣọ́ọ̀bù wà ní títì pa
entertainment
Atiku vs Buhari: Adájọ́ yóò ṣẹ̀dájọ́ lóní lórí ìbò ààrẹ Naijiria
politics
Nigeria swearing-in 2019: Wo àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè nípa ìbúra ààrẹ àtàwọn gómìnà
politics
Aregbesola: Ó se bẹbẹ ní ọdún mẹ́jọ tó fi sèjọba l‘Ọ́sun
politics
Wo àwọn ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun mẹ́tàlá tí àjọ ọ̀hún fọ́nka síta
nigeria
Organisation of Islamic Cooperation: Àǹfààní wo ló wà nínú ẹgbẹ́ OIC?
world
Shiite: Ilé ẹjọ́ gíga Kaduna sún ìgbẹ́jọ́ adarí Shiite síwájú
nigeria